Wednesday , September 27 2023

Wòli láti Gambia gbé owó, ẹ̀rọ ìbànisọ̀rọ̀ àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ sá lọ lẹ́yìn ìsọjí n’Íbàdàn.


A lọ sí àgbègbè Apọ́nrin, Agbowó, ìlú Ìbàdàn, níbi tí oníwàásù Owen Abraham ti ṣe ìsọjí ọlọ́jọ́ márùn-ún, tó sì kó ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀rọ Ìbànisọ̀rọ̀ àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ lọ lẹ́yìn àwọn ìlérí asán tó ṣe fún wọn.

A bá díẹ̀ nínú àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ ọ̀hún sọ̀rọ̀, wọ́n sì sọ bí ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún ṣe ṣẹlẹ̀ gan-an.

All rights reserved. This material, and other digital content on this website, may not be reproduced, published, broadcast, rewritten or redistributed in whole or in part without prior express written permission from NewsTimes247.com.

[email protected]

Check Also

Tribunal dismisses ANPP’s petitions against Akwa Ibom gov, upholds Eno’s election

The Governorship Election Petitions Tribunal sitting in Uyo, Akwa Ibom State, has dismissed the petitions …

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *